a
Mk 12.1-12
;
Lk 20.9-19
;
Isa 5.1-7
.
Matthew 21:33
Òwe àwọn ayálégbé
33
a
“Ẹ gbọ́ òwe mìíràn: Baálé ilé kan tí ó gbin ọgbà àjàrà, ó ṣe ọgbà yìí ká, ó wá ibi ìfúntí sínú rẹ̀, ó kọ́ ilé ìṣọ́. Ó sì fi oko náà ṣe àgbàtọ́jú fún àwọn àgbẹ̀ kan, ó sì lọ sí ìrìnàjò.
Copyright information for
YorBMYO